Cântico da Liberdade
Ìrísí

Cântico da Liberdade (Yorùbá: Orin Òmìnira) jẹ́ orin oríkì orílẹ̀-èdè Cape Verde. Ọdún 1996 ni wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí ń lòó, dípò "Esta É a Nossa Pátria Bem Amada" tó jẹ́ orin oríkì orílẹ̀-èdè Guinea-Bissau náà, nítorí bí orílẹ̀-èdè méjéèjì ṣe jọ gba òmìnira. Amílcar Spencer Lopes ló kọ ọ̀rọ̀ inú orin náà ní ọdún 1948, Adalberto Higino Tavares Silva ló fi ìlànà bí wọ́n ṣe ń kọ orin náà lélẹ̀.[1]
Orin náà leléyìí.
| Àyọkà yìí tàbí apá rẹ̀ únfẹ́ àtúnṣe sí. Ẹ le fẹ̀ jù báyìí lọ tàbí kí ẹ ṣàtúnṣe rẹ̀ lọ́nà tí yíò mu kúnrẹ́rẹ́. Ẹ ran Wikipedia lọ́wọ́ láti fẹ̀ẹ́ jù báyìí lọ. |