Femi Branch

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Femi Branch
Ọjọ́ìbíDavid Babafemi Mauton Osunkoya
(1970-05-14)14 Oṣù Kàrún 1970
Sagamu, Ogun, Nigeria
Orílẹ̀-èdèNigerian
Ọmọ orílẹ̀-èdèNigerian
Iṣẹ́
  • actor
  • playwright
  • poet
  • filmmaker
  • producer
  • director
  • model
  • dramatist
Ìgbà iṣẹ́1991–present
Gbajúmọ̀ fúnAuthor of 409 page Anthology of Fifty Poems and Three Plays titled FROM SENBORA published in Dec. 2010 Producer/Writer of the Movie AWAY FROM HOME (2005)
Notable workFROM SENBORA - an Anthology of Fifty Poems and Three Plays
Ọmọ ìlúOdosenbora
Àwọn ọmọTwo
Parent(s)Ọ̀túba Gbolade & Chief Mrs Modúpẹ́ Ọ̀ṣúnkọ̀yà
Àwọn olùbátanBarr. Olugboyega Osunkoya, Apostle John Benhotons
AwardsSpecial Recognition Award, Ambassadors O. A. U. Ile Ife, Actor of the Year, Moshood Abiola Polytechnic, Ogun State, Special Recognition Award, University of Illorin, African Youth Council Special Recognition.
Websitewww.femibranch.com

Fẹ́mi Babáfẹ́mi Branch ni wọ́n bí ní ọjọ́ Kẹrìnlá oṣù Karùn ún, ọdún 1970 (14-5-1970). Jẹ́ òṣèré Orí-ìtàgé, Yorùbá àti Gẹ̀ẹ́sì,olùkọ̀tàn àti akọ ewì àpilẹ̀kọ , adarí eré àti olùgbéré-jáde ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà .[1][2]

Ibẹ́rẹ́ ayé àti ẹ̀kọ́ rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Wọ́n bí Fẹ́mi ní ìlú Ṣàgámù ní ìpínlẹ̀ Ìpínlẹ̀ Ògùn, sínú ẹbí Ọ̀ṣúnkọ̀yà ní ọdún 1970. Ṣùgbọ́n wọ́n ṣẹ̀ wá láti ìlú Odòṣẹ̀ńbora ní agbègbè ìjọba ìbílẹ̀ Ilá Oòrùn Ìjẹ̀bú. [3] Ó lọ sí ilé-ẹ̀kọ́ alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ́ Satellite Town ní agbègbè ìjọba ìbílẹ̀ Amúwó Ọ̀dọ̀fin,ní Ìpìlẹ̀ Èkó, ṣáájù kí ó tó lọ sí ilé-ẹ̀kọ́ Girama Airforce ní Ìkejà.[4] Lẹ́yìn èyí ni ó lọ sí ilé-ẹ̀kọ́ Ifáfitì Ọbáfẹ́mi Awólọ́wọ̀ níbití ó ti ó ti gba ìwé ẹ̀rí akọ́kọ́ nínú ìmọ Eré Oníṣe.[5]

Àwọn Ìtaọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "TOP ACTOR FEMI BRANCH OPENS UP ON N4M DEBT SCANDAL". nigeriafilms.com. Archived from the original on 25 February 2015. Retrieved 25 February 2015. 
  2. "Nollywood Actor, Femi Branch Play Host @ Miss Insurance Grand Finale -- article". dailytimes.com.ng. Archived from the original on 25 February 2015. Retrieved 25 February 2015. 
  3. Tolu. "Nollywood Actor, Femi Branch, Battles Serious Spiritual Problem…". INFORMATION NIGERIA. Archived from the original on 25 February 2015. Retrieved 25 February 2015. 
  4. "Femi Branch: How Acting Affects Family Life, Articles - THISDAY LIVE". thisdaylive.com. Archived from the original on 25 February 2015. Retrieved 25 February 2015. 
  5. "I have a ministry, but Im not a pastor -Femi Branch". modernghana.com. Retrieved 25 February 2015.