Funmilola Aofiyebi-Raimi

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Funlola Aofiyebi-Raimi
Aofiyebi-Raimi in 2010
Ọjọ́ìbíAbibat Oluwafunmilola Aofiyebi
Orílẹ̀-èdèNigerian
Orúkọ mírànFAR
Iṣẹ́Actress
Ìgbà iṣẹ́1996 Àdàkọ:En dash present
Gbajúmọ̀ fúnTinsel
Olólùfẹ́Olayinka Raimi

Funlola Aofiyebi-RaimiYo-Funlola Aofiyebi-Raimi.ogg Listen tí orúkọ àbísọ rẹ̀ ń jẹ́ Abibat Oluwafunmilola Aofiyebi tí àwọn ènìyàn tún mọ̀ sí FAR, jẹ́ òṣèrébìnrin ti orílè-èdè Nàìjíríà. Ó ti ṣàfihàn nínú àwọn fíìmù bí i The Figurine, Tinsel àti MTV Shuga.

Ìgbésí ayé rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Funlola jẹ́ ọmọ àbígbẹ̀yìn àwọn òbí ọlọ́mọ méje. Ìyá rè jẹ́ onísòwò, bàbá rẹ̀ sì jẹ́ olùdókòwò. Orúkọ FAR tí wọ́n ń pè é mọ́ ọn lórí nígbà tí ó ṣe ìgbéyàwó. FAR tètè farahàn lórí ẹ̀rọ-amóhùnmáwòrán pẹ̀lú àǹtí rẹ̀ Teni Aofiyebi, tó jẹ́ àgbà òṣèré.[1] Ó fẹ́ olùṣèpolówó ọjà tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Olayinka Raimi. Látàrí ikú ẹ̀gbọ́n rè, ó pinnu láti yẹra fún ẹ̀rọ-ayélujára fún ìgbà díẹ̀, ó sì padà.[2]

Àtòjọ àwọn àmì-ẹ̀yẹ rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Awards[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ọdún Àmì-ẹ̀yẹ Ìsọ̀rí Èsì Ìtọ́ka
2010 Africa Movie Academy Awards (AMAA) Best Actress in a Supporting Role (Figurine) Wọ́n pèé
Nigeria Entertainment Awards Best Actress in a TV Show (Tinsel) Wọ́n pèé
2017 Best of Nollywood Awards Best Supporting Actress –English Wọ́n pèé [4]
2018 Best of Nollywood Awards Best Actress in a Lead Role - English Wọ́n pèé [5]

Àwọn ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. Suleiman, Yemisi (30 August 2009). "I've always wanted to educate and entertain people - Funlola Aofiyebi-Raimi". Vanguard. Retrieved 29 September 2013. 
  2. "Actress Funlola aofiyebi-Raimi returns to social media after 3-month break to mourn late brother". Vanguard News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2 August 2021. Retrieved 22 July 2022. 
  3. O'Kelly, Aoife (9 October 2019). "Walking with Shadows". Oya Media. Retrieved 23 May 2021. 
  4. "BON Awards 2017: Kannywood’s Ali Nuhu receives Special Recognition Award". Daily Trust (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 23 November 2017. Retrieved 7 October 2021. 
  5. "BON Awards 2018: Mercy Aigbe, Tana Adelana shine at 10th edition". Pulse Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 9 December 2018. Retrieved 23 December 2019.