Kalakuta Republic

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Kalakuta Republic ni oruko ti olorin ati ajafun oloselu tiwatiwa, Fẹla Kuti fun ni agbowo ilé ti ohun, àwon ebí rè àti àwon omo egbé olorin rè wa, ibè náà ni ilé orin rè wa. Ilé náà wa ni 14 Agege Motor Road, Idi-Oro, Mushin, ìpinlè Èkó, Naijiria, o ni ile-iwosan ọfẹ Fẹla sọ pe ilé náà ko sí lábé ìjoba Ologun junta leyin ti o pada lati Amẹrika ni ọdun 1970. Ogba naa jona ni 18 February 1977 ìgbà tí awon ọmọ ologun bi egbèrún se ìkolù si.[1]

Fela so ilé náà ni "kalakuta" láti se yeye ogbà ewon "Calcutta tí o ti sùn rí. Kí o dipé wón wo ilé náà, Fela ko orin kan nípa ìjoba ologun, o pe oruko orin náà ní "Zombie". Nínú orin náà, o se yèyé àwon ologun pé won Ma un tèlé ìjoba ologun láì ronú. [2]

Orin náà gbajúmọ̀ gan ní Nàìjíríà, ó sì bí Olórí ologun ní Nàìjíríà, Ọ̀gágun Olusegun Obasanjo nínú.

nígbà náà. Inu awọn ọmọ ogun ko dun si bi Fẹlse un n ṣe ariwissiwon n nigba gbogbo, wọn si sọ pe ko bojumu lati ni ijọbolominira tirare ninú orílè-èdè a olominian. Awọiroyin kan ní d Naijiriba ún bèrè si ún gbé itan jan tí wón òle jeri sí pé wón ma un tan àwon n ọbirin lo ogba Fela ti àwon omo egbé Fela kuti si ún mú won se ìkan tí ko da.

Nígbà tí awọn ọmọ ogun Naijiria se ìkolù sí Kalakuta Republic, wón ju iya Fẹla Frances Abigail Olufunmilayo Thomas jáde láti pètésì kejì lati oju ferese sílè.Ìyá rè ku lẹhin ti o wa ni kíkú-yíyè fun bii ọsẹ mẹjọ.[3]

Àwon ìtókasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "Home". Kalakuta Museums. 2020-11-09. Retrieved 2022-09-11. 
  2. Fela: The Life and Times of an African Musical Icon. p. 143. 
  3. "Fela Kuti: Chronicle of A Life Foretold". The Wire (169). September 2011. http://www.thewire.co.uk/in-writing/essays/fela-kuti_chronicle-ofa-life-foretold. Retrieved 2015-06-13.