Niche

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

 

TheNiche jẹ́ ìwé-ìròyìn orí ayélujára ójóójúmọ̀ tí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí ìṣètò ní 20 oṣù Kẹrin ọdún 2014, ní Ikeja, Ìpínlẹ̀ Èkó . TheNiche tí forúkọsílẹ lábẹ́ Àwọn ilé-iṣẹ àti Òfin Àwọn ọrọ tì 1990 àti pé ó jẹ atẹjáde nípasẹ̀ Acclaim Communications Limited. [1] [2]

Ìtàn[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

TheNiche jẹ ìwé ìròyìn orí ayélujára tí ó dá nípasẹ̀ àwọn óníṣé ìròyìn Nàìjíríà-Alàkòsò àti olùdarí / ólóótú ni olórí Ikechukwu Amaechi, Eugene Onyeji, Emeka Duru àti Kehinde Okeowo. TheNiche bẹrẹ̀ ìkéde ni 20 oṣù Kẹrin ọdún 2014.

Ní ọdún 2018, àjọ náà ṣètò ipilẹ TheNiche fún Ìdàgbàsókè Ìwé ìròyìn ní ilépá àwọn ìpìlẹ̀ wọnyí. [3]

Àwọn atẹjadé kẹta àti kẹrin ní ọdún 2020 àti 2021 kò dúró nítorí ájákáye-àrùn COVID-19

Ní ọdún 2022, àjọ náà fí Babatunde Fashola, Kingsley Moghalu, Anya Oko Anya, Christopher Kolade, Remi Sonaiya àti Tanko Yakasai sínú ẹgbẹ́ gbajúmọ èniyàn rẹ, ọlá tí á fí pamọ fún àwọn ẹní-kọọkan tí ó sọ ọrọ̀ lórí ìkọ̀wé lọ́dọọdún TheNiche tàbí ṣé bí àwọn alága. [4] [5]

ìkọ̀wé lọọdọdún TheNiche[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

TheNiche Oun ní Ọdọọdún ìkọ̀wé gbogbo ọdún làti sọ̀rọ̀ àwọn orílẹ̀-èdè ilé ajé àti ìjọba tíwáńtíwá.

Ní ọjọ́ kẹjọ oṣù Kẹ̀sán ọdún 2022, [6] Babatunde Fashola, mínísìítá fún ètò ìṣe àti ilé Nàìjíríà, jíròrò lórí ìdìbò Nàìjíríà 2023 àti ọjọ́ iwájú ìjọba tíwáńtíwà Nàìjíríà ní ìkéde 2022 tí ìkọ̀wé lọdọọdún TheNiche. [7] [8]

Àwọn itọkàsì[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. Oyewole, Nurudeen (2014-08-31). "Launch of TheNiche newspaper attracts praises, goodwill". Archived from the original on 2014-09-01. https://web.archive.org/web/20140901234757/http://www.dailytrust.com.ng/sunday/index.php/media-media/17965-launch-of-theniche-newspaper-attracts-praises-goodwill. 
  2. "About Us". https://www.thenicheng.com/about-us/. 
  3. "Development Reporting Takes Centre Stage as TheNiche Holds Anniversary Lecture". This Day. 2018-04-19. https://www.thisdaylive.com/index.php/2018/04/19/development-reporting-takes-centre-stage-as-theniche-holds-anniversary-lecture/. 
  4. Ajiboye, Kayode (2022-10-04). "TheNiche Inducts Fashola, Yakasai, Kola, Anya, Sonaiya, Moghalu Into Its Hall Of Fame". Independent Nigeria. https://independent.ng/theniche-inducts-fashola-yakasai-kola-anya-sonaiya-moghalu-into-its-hall-of-fame/. 
  5. "On TheNiche Hall of Fame By Eugene Onyeji". Sundiata Post. 7 October 2022. https://sundiatapost.com/on-theniche-hall-of-fame-by-eugene-onyeji/. 
  6. Oguntola, Tunde (2022-09-08). "TheNiche Annual Lecture Holds Today". Leadership. https://leadership.ng/theniche-annual-lecture-holds-today/. 
  7. "Fashola, others speak on future of Nigeria's democracy at 2022 TheNiche lecture". Vanguard. 5 September 2022. https://www.vanguardngr.com/2022/09/fashola-others-speak-on-future-of-nigerias-democracy-at-2022-theniche-lecture/. 
  8. Shibayan, Dyepkazah (6 September 2022). "Fashola to speak on Nigeria's democracy at TheNiche's annual lecture on Thursday". TheCable. https://www.thecable.ng/fashola-to-speak-on-nigerias-democracy-at-theniches-annual-lecture-on-thursday.