Oluwarotimi Odunayo Akeredolu
Jump to navigation
Jump to search
Ọlọ́lájùlọ Oluwarotimi Odunayo Akeredolu | |
---|---|
![]() Oluwarotimi Akeredolu ní ọdún 2016 | |
Gómìnà Ìpínlẹ Ondo | |
Lọ́wọ́lọ́wọ́ | |
Ó gun orí àga ọjọ́ kẹfàdínlọ́gbọn oṣù kejì ọdún 2017 | |
Asíwájú | Olusegun Mimiko |
Àwọn àlàyé onítòhún | |
Ọjọ́ìbí | Oluwarotimi Odunayo Akeredolu 21 Oṣù Keje 1956 Owo, Ìpínlẹ Ondo |
Ọmọorílẹ̀-èdè | Orílẹ̀ edè Nàijíríà |
Ẹgbẹ́ olóṣèlú | All Progressives Congress |
(Àwọn) olólùfẹ́ | Betty Anyanwu-Akeredolu |
Alma mater | Obafemi Awolowo University |
Occupation | Olóṣèlú agbẹjọ́rò |
Website | aketi.org |
Oluwarotimi Odunayo Akeredolu, SAN, or Rotimi Akeredolu, (ọjọ́ ìbí 21 July 1956) jẹ́ olóṣèlú àti agbẹjọ́rò ará Nigeria tó jẹ́ Gómìnà Ìpínlẹ Ondo ní orílẹ̀ edè Nàijíríà lọ́wọ́lọ́wọ̣́. [1] Akeredolu tún jẹ́ ìkan nínú àwọn agbẹjọ́rò àgbà ti ilẹ̀ Nàìjíríà (SAN) tí ó sì jẹ́ ààrẹ ẹgbẹ́ amòfin ti orílẹ̀ edè Nàijíríà ní ọdún 2008.[2]
Àwọn ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
- ↑ "Breaking Ondo decides Inec officially declares Rotimi Akeredolu Governor elect". www.premiumtimesng.com. Retrieved 27 November 2016.
- ↑ "Nigerian Bar". www.nigerianbar.org. Retrieved 27 November 2016.