Adésọjí Adérẹ̀mí
Jump to navigation
Jump to search
Adesoji Tadeniawo Aderemi | |
---|---|
Governor of Western Region | |
In office 1960–1967 | |
Asíwájú | Obafemi Awolowo |
Arọ́pò | Samuel Ladoke Akintola |
Oba of Ife | |
In office 1930 – 7 July 1980 | |
Asíwájú | Ademiluyi Ajagun |
Arọ́pò | Okunade Sijuwade |
Àwọn àlàyé onítòhún | |
Ọjọ́ìbí | 15 November 1889 |
Aláìsí | 7 July 1980 |
Adésojí Adérèmí (15 November 1889 – 7 July 1980) je Ọ̀ọ̀ni Ilé Ifẹ̀ lati odun 1930 de 1980. Ohun tun ni Gomina Agbegbe Apaiwoorun ile Naijiria.
Oriki[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
Emó kú ojú òpó dí. Afèèbòjò kú, enu isà ń sòfò Ohun Ekùn ti lo. Oba nÍfè Onòni. Ikú ò meni à á pa, òjò ò mẹni ọ̀wọ̀. Òjò ìbá meni òwò ni, Ìbá tí poníSàngó, Ìbá tí POlóya.
Kááábíyèsí!...
- S.M. Raji (2003), Igi Ń dá Lektay Publishers, Ibadan, Oju-ìwé 98-101.
![]() |
Àyọkà yìí tàbí apá rẹ̀ únfẹ́ àtúnṣe sí. Ẹ le fẹ̀ jù báyìí lọ tàbí kí ẹ ṣàtúnṣe rẹ̀ lọ́nà tí yíò mu kúnrẹ́rẹ́. Ẹ ran Wikipedia lọ́wọ́ láti fẹ̀ẹ́ jù báyìí lọ. |