Emily Nkanga

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Emily Nkanga
Emily Nkanga ní London ní ọdún 2017
Ọjọ́ìbíEmily Oluwatobi Nkanga
21 Oṣù Kàrún 1995 (1995-05-21) (ọmọ ọdún 28)
Ìpínlẹ̀ Èkó, Nàìjíríà
Iṣẹ́Ayàwòrán
Ìgbà iṣẹ́2012 títí di ìsinsìnyí
Websiteemilynkanga.com

Emily Nkanga jẹ́ ayàwòrán ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà àti Ilẹ̀ọba Aṣọ̀kan, ó tún ń ṣe fíìmù jáde. Nkanga gbajúmọ̀ fún iṣẹ́ rẹ̀ pẹ̀lú àwọn olórin bi Koker, Aramide, Boj, Olamide, Jidenna, Not3s,[1] Mr Eazi, Mayorkun, Adekunle Gold, Sarz, òṣèré Adesola Osakalumi, agbábọ́ọ̀lù Tammy Abraham àti Femi Kuti.[2] Ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn àwòrán Nkanga jẹ́ nípa àwọn ènìyàn tí wón ti pàdánù ilé àti ọ̀nà wọn ní àríwá Nàìjíríà nítorí ogun Boko Haram.[3]

Ìpìlẹ̀ àti Ẹ̀kọ́ rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Wọ́n bí Nkanga ní ìpínlẹ̀ Èkó sínú ìdílé Idongesit àti Mosunsola Nkanga, Ìpínlẹ̀ Èkó náà ni wọ́n ti tọ dàgbà. Ó lọ ilé-ìwé Air Force Girls Comprehensive School, Jos, Ìpínlẹ̀ Plateau, lẹyìn náà, ó tẹ ẹ̀kọ́ rẹ̀ síwájú ní American University of Nigeria, Yola, Ìpínlẹ̀ Adamawa, ní Àríwá Nàìjirià.[4] Ó ni àmì ẹyẹ masters of art nínú ṣíṣe àgbéjáde láti Yunifásitì Goldsmiths ti London.

Àwọn Ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "Why British artist Not3s is the hottest sound of this summer". GQ Magazine (London, England). 6 July 2018. https://gq-images.condecdn.net/image/olb7pOMAYGr/crop/810/f/notes-01-gq-27jun18_b.jpg. Retrieved 10 November 2018. 
  2. Soni, Daniel (22 May 2016). "Like my pilot-father, I also dream to conquer the world – 21-yr-old Emily Nkanga". The Vanguard Newspaper (Lagos, Nigeria). http://www.vanguardngr.com/2016/05/like-pilot-father-also-dream-conquer-world-21-yr-old-emily-nkanga/. Retrieved 5 June 2017. 
  3. Orubo, Daniel (26 September 2016). "Photographer Takes Powerful Images Of People Displaced By Boko Haram In Northeast Nigeria". Konbini (Lagos, Nigeria). Archived from the original on 18 September 2016. https://web.archive.org/web/20160918070756/http://www.konbini.com/ng/inspiration/this-photographer-took-powerful-images-of-people-displaced-by-boko-haram-in-northeast-nigeria/. Retrieved 5 June 2017. 
  4. "Choosing photography as a career, very challenging — Emily Nkanga". The Vanguard Newspaper (Lagos, Nigeria). 22 June 2016. http://www.vanguardngr.com/2016/06/choosing-photography-career-challenging-emily-nkanga/. Retrieved 6 June 2017.