Foreigner's God (fiimu)
Ìrísí
Foreigner's God (fiimu) | |
---|---|
Adarí | Ifan Ifeanyi Michael |
Olùgbékalẹ̀ | Kelechi Freeman Ukadike |
Àwọn òṣèré | Henry Coxe, Ini Dima-Okojie, Toni Tones, Pete Edochie, Bambam (Oluwabamike Olawumi), Teddy A (Tope Teddy Adenibuyan), Eucharia Anunobi, Sam Dede, Toyin Abraham. |
Ilé-iṣẹ́ fíìmù | Ifan Micheal Productions |
Déètì àgbéjáde |
|
Orílẹ̀-èdè | Nigeria |
Èdè | English |
Foreigner’s God jẹ́ fíìmù ọdún 2019, èyí tí Kelechi Freeman Ukadike ṣàgbéjáde, tí Ifan Ifeanyi Michael sì darí lábẹ́ ilé-iṣẹ́ Ifan Micheal Productions.[1][2] Lára àwọn òṣèré tó kópa nínú fíìmù yìí ni Henry Coxe, Ini Dima-Okojie, Toni Tones, Pete Edochie, Nkem Owoh, Bambam (Oluwabamike Olawumi), Teddy A (Tope Adenibuyan), Eucharia Anunobi, Sam Dede, Toyin Abraham, Salma Mumin, àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ.[3][4]
Ìtàn ní ṣókí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Eré yìí dá lórí ayàwòrán ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì kan, tó wá sí ilẹ̀ Íbò lásìkò ìjọba amúnisìn. Àyípadà dé bá eré náà nígbà tí ẹ̀ṣọ́ rẹ̀ ṣàdẹ́dé di àwátì, tí í sì padà wá nífẹ̀ẹ́ ọmọbìnrin àjẹ́ kan tí ń gbé nínú igbó.[4][1][2]
Amazon Prime Video
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Bí ó tilẹ̀ jé pé wọ́n ṣàgbéjáde fíìmù náà ní ọdún 2019, ọdún 2022 ni wọ́n gbe sí orí Amazon Prime Video.[1]
Àwọn òṣèrẹ́ tó kópa
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- Henry Coxe[3]
- Ini Dima-Okojie
- Toni Tones, Bambam (Oluwabamike Olawumi)
- Teddy A (Tope Adenibuyan)[4]
- Pete Edochie
- Nkem Owoh
- Sam Dede
- Eucharia Anunobi
- Toyin Abraham
- Lala Akindoju
- Kunle Idowu
- Sharon Ooja
- Linda Osifo
- Yinka Pierce-Tijani
- Annie Idibia[5]
Àwọn ìtọ́kasí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ 1.0 1.1 1.2 Nwogu, Precious 'Mamazeus' (2022-05-10). "Ifan Michael's 'Foreigner's God' acquired by Amazon Prime". Pulse Nigeria. Retrieved 2022-07-26.
- ↑ 2.0 2.1 "Bambam and Teddy A secure roles in 'Foreigner's God' – The Eagle Online" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2 May 2018. Retrieved 2022-07-26.
- ↑ 3.0 3.1 "Movie Fans Await Ifan Michael's 'Foreigner's God' – THISDAYLIVE". www.thisdaylive.com. Archived from the original on 2022-07-26. Retrieved 2022-07-26. Unknown parameter
|url-status=
ignored (help) - ↑ 4.0 4.1 4.2 Augoye, Jayne (2018-05-02). "#BBnaija: Teddy A, Bambam land Nollywood roles". Premium Times Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2022-07-26.
- ↑ "And It's BamTeddy For Nollywood In Foreigner's God". Independent Newspaper Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2018-05-05. Retrieved 2022-07-26.