Wọlé Sóyinká
(Àtúnjúwe láti Wole Soyinka)
Jump to navigation
Jump to search
Wọlé Sóyinká | |
---|---|
![]() Wole Soyinka in 2018 | |
Ọjọ́ ìbí | Akínwándé Olúwolé Babátúndé Sóyíinká[1] 13 Oṣù Keje 1934 Abeokuta, Nigeria Protectorate (now Ogun State, Nigeria) |
Iṣẹ́ |
|
Ọmọ orílẹ̀-èdè | Nigerian |
Ẹ̀kọ́ | Abeokuta Grammar School University of Leeds |
Ìgbà | 1957–present |
Genre |
|
Subject | Comparative literature |
Notable awards | Nobel Prize in Literature 1986 Academy of Achievement Golden Plate Award 2009 |
Akinwande Oluwole Babatunde Soyinka (ọjọ́ìbí 13 July 1934) jẹ́ ọ̀jọ̀gbọ́n (Professor) nínú Ìmọ̀ Lítíréṣọ̀ (literature), alákọsílẹ̀, eré orí ìtàgé (playwright) ati akéwì (poet). Wọlé Sóyinká jẹ́ ògidì ọmọ Yorùbá lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Ó gba Ẹ̀bùn Nobel ní ọdún 1986 fún iṣẹ́ owo re lori igbega imo ikowe.[2].
Ìgbà èwe àti aáyan ìkẹ́kọ̀ọ́ rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
Wọ́n bí Wọlé Sóyinká ní ìlú Abẹ́òkúta, ní ìpínlẹ̀ Ògùn, Lẹ́yìn tí ó parí ẹ̀kọ́ rẹ̀ ní orílè-èdè Nàìjíríà àti United Kingdom tán, Ó ṣiṣẹ́ pẹ̀lú Theatre Royal Court ni ìlú Loọ́ńdọ̀nù (London). Ó tẹ̀ síwájú láti kọ àwọn eré oníṣe lorílẹ̀ èdè méjèèjì ní tíátà àti orí ẹ̀rọ Asọ̀rọ̀-mágbèsì. Ó kó ipa pàtàkì nínú ètò ìṣèlú àti akitiyan lópọ̀lọpọ̀ nínú ìjàǹgbara òmìnira orílẹ̀ èdè Nàìjíríà kúrò lọ́wọ́ ìjọba amúnisìn Great Britain.[3]
Àwọn Ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
- ↑ Tyler Wasson; Gert H. Brieger (1 January 1987). Nobel Prize Winners: An H.W. Wilson Biographical Dictionary, Volume 1. The University of Michigan, U.S.A. p. 993. ISBN 9780824207564. https://books.google.com/?id=hpQYAAAAIAAJ&dq=born+Oluwole+Babatunde+Akinwande+Soyinka. Retrieved 4 December 2014.
- ↑ "The Nobel Prize in Literature 1986". NobelPrize.org. 1986-12-10. Retrieved 2019-09-19.
- ↑ Laureate., the (1934-07-13). "The Nobel Prize in Literature 1986". NobelPrize.org. Retrieved 2019-09-09.