Bọ́lájí Akínyẹmí

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
(Àtúnjúwe láti Bolaji Akinyemi)
Bolaji Akinyemi
External Affairs Minister of Nigeria
In office
1985–1987
ÀàrẹIbrahim Babangida
AsíwájúIbrahim Gambari
Arọ́pòIke Nwachukwu
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbíJanuary 4, 1942
Ilesa, Osun State
Ọmọorílẹ̀-èdèNigerian
(Àwọn) olólùfẹ́Rowena Akinyemi
Àwọn ọmọAtinuke Akinyemi, Tosin Akinyemi, Tolu Akinyemi, Benjamin Akinyemi
ProfessionProfessor of political science
Websitewww.profbolajiakinyemi.com

Akínwándé Bọ́lájí Akínyẹmí tí wọ́n bí ní Ọjọ́ kẹrin oṣù kìíní ọdún 1942 (January 4, 1942) jẹ́ ọ̀jọ̀gbọ́n onímọ̀ sáyẹ́nsì, olóṣèlú ọmọ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà[1] to di Alakoso Oro Okere Naijiria lati 1985[2] titi de opin 1987.[3] Ohun ni Alaga National Think Tank.[4]



Àwọn Ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. Shaw, Timothy M.; Julius Omozuanvbo Ihonvbere. Illusions of Power: Nigeria in Transition. Africa World Press. p. 190. ISBN 0865436428. 
  2. Oloyede, Dokun (2002-01-06). "Bolaji Akinyemi, the Seagull, at 60". Thisday online (Leaders & Company). Archived from the original on 2007-12-08. https://web.archive.org/web/20071208041700/http://www.thisdayonline.com/archive/2002/01/06/20020106tri01.html. Retrieved 2007-10-27. 
  3. Shaw, 127.
  4. "National Think Tank pledges support for Omehia". The Tide Online (Rivers State Newspaper Corporation). 2007-10-10. http://www.thetidenews.com/article.aspx?qrDate=10/10/2007&qrTitle=National%20Think%20Tank%20pledges%20support%20for%20Omehia&qrColumn=FRONT%20PAGE. Retrieved 2007-10-27.