Ìpínlẹ̀ Kaduna

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
(Àtúnjúwe láti Ipinle Kaduna)
Kaduna State
Nickname(s): 
Location of Kaduna State in Nigeria
Location of Kaduna State in Nigeria
Country Nigeria
Date created27 May 1967
CapitalKaduna
Government
 • Governor
(List)
Nasir Ahmad El-Rufai (APC)
Area
 • Total46,053 km2 (17,781 sq mi)
Area rank3rd of 36
Population
 (2006 census)1
 • Total6,066,562
 • Rank3rd of 36
 • Density130/km2 (340/sq mi)
GDP (PPP)
 • Year2007
 • Total$10.33 billion[1]
 • Per capita$1,666[1]
Time zoneUTC+01 (WAT)
ISO 3166 codeNG-KD
^1 Preliminary results

Ìpínlẹ̀ Kàdúná jẹ́ ọ̀kan nínú àwọn Ìpínlẹ̀ mẹ́rìdínlógójì ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Ìpínlẹ̀ Kàdúná jẹ́ ọkan lára ìpínlẹ̀ tó wà ní apá Àríwá orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Olú-ìlú ìpínlẹ̀ yìí ń bá a jórúkọ, ìlú Kàdúná, èyí tí ó jẹ́ ìlú kẹ́jọ tí ó tóbi jù ní orílẹ̀-èdè yìí ní ọdún 2006. Wọ́n dá ìpínlẹ̀ yìí sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bí Ìpínlẹ̀ àárín-gbùngbùn Àríwá ní ọdún 1967, èyí tí ó yíká Ìpínlẹ̀ Katsina òde-òní. Ní ọdún 1987 ní Ìpínlẹ̀ Kàdúná ṣẹ ààlà-ọ̀nà wọn. Ìnagijẹ Kàdúná ní Center of learnig (Ilé fún ẹ̀kọ́). Orúkọ yìí ṣe rẹ́gí wọn Nítorí ọ̀pọ̀ ilé-ẹ̀kọ́ tó ní kìmí ni ó wà ní ìpínlẹ̀ náà, àpẹẹrẹ ní Ahmadu Bello University.[2]

Ìpínlẹ̀ Kàdúná òde-òní jẹ́ ilé ìṣura fún àwọn ohun ìlàjú ilẹ̀ Áfíríkà, kódà, Nok civilization tí ó gbèrú láti c.1500 BC sí c. 500 AD náà wà ní bẹ̀.[3][4] Ní séntúrì 9th, òwúlẹ̀-wútàn tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Ya'qubi ṣe àkọsílẹ̀ ìwàláyé Ìjọba Hausa, èyí tí ó wà kí wón tó sọ ọ́ di Sokoto Caliphate ní ọdún 1800 lẹ́yìn ìjà àwọn Fulani.[5] Ní àkókò ìmúnisìn, àwọn olùdarí ilẹ̀- Britain sọ Kàdúná di olú-ìlú Àbọ̀ ní Àríwá orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.


Itokasi[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. 1.0 1.1 "C-GIDD (Canback Global Income Distribution Database)". Canback Dangel. Retrieved 2008-08-20. 
  2. Àṣìṣe ìtọ́kasí: Invalid <ref> tag; no text was provided for refs named :1
  3. Breunig, Peter. 2014. Nok: African Sculpture in Archaeological Context: p. 21.
  4. Fagg, Bernard. 1969. Recent work in west Africa: New light on the Nok culture. World Archaeology 1(1): 41–50.
  5. Nwabara, Samuel (1963). "The Fulani conquest and rule of the Hausa Kingdom of Northern Nigeria (1804–1900)". Journal des Africanistes 33 (2): 231–242. doi:10.3406/jafr.1963.1370. https://www.persee.fr/doc/jafr_0037-9166_1963_num_33_2_1370. Retrieved 8 December 2021.