Marcus Garvey
Marcus Garvey | |
---|---|
![]() Garvey in 1924
|
|
Ọjọ́ìbí | Marcus Mosiah Garvey, Jr. 17 Oṣù Kẹjọ 1887 St. Ann's Bay, Jamaica |
Aláìsí |
10 Oṣù Kẹfà, 1940 (ọmọ ọdún 52) London, England, UK |
Iṣẹ́ | Publisher, journalist |
Known for | Activism, Black Nationalism, Pan-Africanism |
Children | Marcus Mosiah Garvey, III (born 17 September 1930) ati Julius |
Parent(s) | Marcus Mosiah Garvey, Sr. Sarah Jane Richards |
Marcus Mosiah Garvey, Jr., ONH (17 August 1887 – 10 June 1940)[1] je atewejade, oniroyin, onisowo, ati olohun ara Jamaika to da aba irinkankan Iseolomoorile-ede Adulawo ati Ise Gbogbo Afrika, nitoe to fi da Egbe Igbesoke Adulawo Agbalaaye ati Egbe awon Agbajo Afrika (UNIA-ACL).[2] O seidasile ile-ise Black Star Line, bi apa eto Ipada si Afrika, to poloungo ipada lo si Afrika gbogbo awon Omo Afrika Leyin-odi.
![]() |
Àyọkà yìí tàbí apá rẹ̀ únfẹ́ àtúnṣe sí. Ẹ le fẹ̀ jù báyìí lọ tàbí kí ẹ ṣàtúnṣe rẹ̀ lọ́nà tí yíò mu kúnrẹ́rẹ́. Ẹ ran Wikipedia lọ́wọ́ láti fẹ̀ẹ́ jù báyìí lọ. |
Itokasi[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
- ↑ Encyclopedia Britannica Online Marcus Garvey profile. Retrieved 20 February 2008.
- ↑ "The "Back to Africa" Myth". UNIA-ACL website. 14 July 2005. Archived from the original on 30 December 2006. Retrieved 2007-04-01.