Jalingo

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Jalingo
Afárá kan ní agbègbè Jalingo
Orílẹ̀-èdè Nigeria
IpinleTaraba
Agbegbe Ijoba IbileJalingo

Jalingo ni olú-ìlú Ìpínlẹ̀ Taraba ní ariwa ìwọ oòrùn Nàìjíríà , Jalingo ní èdè fulfulde túmọ̀ sí "ibi gíga", ó sì ní olùgbé 418,000. Àwọn Fulani àti àwọn ẹ̀yà kẹ́kẹ̀ kẹ́ mìíràn ni ó wà ní ìlú Jalingo.[1] Fulfulde, Mumuye, Hausa àti àwọn èdè míràn ni wọ́n ń sọ ní Jalin

Alámòjútó Alága[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ìjọba ìbílè kọ̀ọ̀kan ní Nàìjíríà lóní alámòjútó alága tó ń darí wọn. Àwọn ni wọ́n ń darí ètò ìpílẹ̀.

Alága tí wọ́n yàn ní Jalingo ní ètò ìdìbò 2020 tó kọjá[2] ni Hon. Abdulnaseer Bobboji ti ẹgbẹ́ òṣẹ̀lú People Democratic Party (PDP).[3] Ó ti jẹ́ alámòjútó alága títí tó fi parí àsìkò rẹ̀ ní ọjọ́ Àìkú, oṣù kéje, ọdún 2022.[4][5] gómínà ipínlẹ̀ Taraba Arch. Darius Dickson Ishaku yan aṣojú ètò-ìlera Primary Health Care Development Agency Alh. Aminu Jauro gẹ́gẹ́ bí alámòjútó alága tí Jalingo.[6][7]

Ọjà[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Jalingo jẹ́ olú-ìlú ìpínlẹ̀ Taraba ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọjà ṣùgbọ́n àwọn ọjà tó gbajúmọ̀ jù.

  • Jalingo Main Market[8]
  • Kasuwan Yelwa (Yelwa Market)[9]


Àwọn Ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "The World Gazeteer". Archived from the original on 2013-02-09. Retrieved 2007-04-06.  Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  2. Royal, David O. (2020-06-09). "Taraba holds LG election June 30". Vanguard News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2022-12-31. 
  3. Report, Agency (2017-02-27). "PDP sweeps elections in Taraba, Gombe, Rivers". Premium Times Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2022-12-31. 
  4. admin (2022-07-03). "PRESS RELEASE: Gov. Ishaku Approves the Dissolution of Local Government Councils". TARABA STATE GOVERNMENT (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Archived from the original on 2022-12-31. Retrieved 2022-12-31. 
  5. admin (2022-07-01). "PRESS RELEASE: LGA Chairmen, Councillors Tenures Ends in Few Days". TARABA STATE GOVERNMENT (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Archived from the original on 2022-12-31. Retrieved 2022-12-31. 
  6. NNN (2022-09-06). "Ex-Taraba primary healthcare secretary assumes office as LG chairman". NNN (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2022-12-31. 
  7. admin (2022-07-03). "PRESS RELEASE: Gov. Ishaku Approves the Dissolution of Local Government Councils". TARABA STATE GOVERNMENT (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Archived from the original on 2022-12-31. Retrieved 2022-12-31. 
  8. "Fuel scarcity, high food prices, others may mar Yuletide in Taraba". The Guardian Nigeria News - Nigeria and World News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2022-12-23. Retrieved 2022-12-31. 
  9. says, Babalola James Olatunde (2022-08-19). "Mu’azu Jaji Sambo, an Unassuming Achiever" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2022-12-31.