Ogun Abẹ́lé Nàìjíríà
Ogun Abẹ́lé Nàìjíríà | |||||||
---|---|---|---|---|---|---|---|
![]() Orileijoba alominira Orile-ede Olominira ile Biafra ni Osu Kefa 1967. | |||||||
| |||||||
Àwọn agbógun tira wọn | |||||||
![]() ![]() Supported by:[1][2] |
Àdàkọ:Country data Biafra
Mercenaries | ||||||
Àwọn apàṣẹ | |||||||
![]() ![]() ![]() ![]() |
Àdàkọ:Country data Biafra Odumegwu Ojukwu Àdàkọ:Country data Biafra Philip Effiong | ||||||
Òfò àti ìfarapa | |||||||
200,000 Military and civilian casualties | 1,000,000 Military and civilian casualties |
Ogún Abẹ́lé Nàìjíríà wáyé láàárín ọjọ́ Kẹfà Oṣù Okúdù Ọdún 1967 sí ọjọ́ kẹẹ̀dógún oṣù Ṣẹ́ẹ́rẹ́: tí a tún mọ̀ sí (Ogun Nàìjíríà - Biafra tàbí Ogun Biafra) jẹ́ Ogun Abẹ́lé tí ó wáyé láàárín ìjọba Nàìjíríà àti orílè-èdè Biafra, Ìpínlẹ̀ tí ó fé dádúró tì ó ti fẹ́ gba òmìnira kúrò lára Nàìjíríà ní ọdún 1967. Ọgágun Yakubu Gowon ni ó ń darí Orílẹ̀èdè Nàìjíríà Lt. Colonel Odumegwu Ojukwu sí ń darí Biafra. Èròngbà àwọn olùfẹ́ ẹ̀yà Ìgbò tí wọ́n rò pé àwọn kò lè bá ìjọba àpapọ̀ ṣe mọ torí pé àwọn Mùsùlùmí ẹ̀yà Haúsá-Fúlàní tí àríwá Orílẹ̀èdè tí jẹ gàba ní Biafra. Ìyọrísí ìkọlù yìí láti rògbòdìyàn ìṣèlú, ọrọ̀ ajé, ẹ̀yà, ajẹmáṣà àti ẹ̀sìn ló bí pínpín Nàìjíríà láti ọdún 1960 sí 1963. Lára àwọn aṣokùnfà ogun ní ọdún 1966 ni ìjà ẹ̀sìn àti ìṣègbè ẹ̀yà Ìgbò ní Apá Àríwá Nàìjíríà. Ìdìtẹ̀gbàjọba, àti ìrẹ́jẹ àwọn Ìgbò ní apá àríwá Naijiria. Bákan náà Ìjẹgàba lórí ìgbéjáde epo rọ̀bì tó lére gọbọi lórí ní Niger Delta náà kópa ribiribi.
![]() |
Àyọkà yìí tàbí apá rẹ̀ únfẹ́ àtúnṣe sí. Ẹ le fẹ̀ jù báyìí lọ tàbí kí ẹ ṣàtúnṣe rẹ̀ lọ́nà tí yíò mu kúnrẹ́rẹ́. Ẹ ran Wikipedia lọ́wọ́ láti fẹ̀ẹ́ jù báyìí lọ. |