Kunle Afolayan

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Kunle Afolayan
Ọjọ́ìbí30 Oṣù Kẹ̀sán 1974 (1974-09-30) (ọmọ ọdún 49)
Ebute Metta, Lagos State, Nàìjíríà
IbùgbéMagodo, Ikeja, Lagos State, Nàìjíríà
Orílẹ̀-èdèNàìjíríà
Iṣẹ́
Olólùfẹ́Tolu Afolayan
Àwọn ọmọ4
Parent(s)Ade Love - father
Àwọn olùbátan

Kunle Afolayan (tí wọ́n bí ní ọjọ́ ọgbọ̀n oṣù kẹsàn-án ọdún 1974) jẹ́ gbajúmọ̀ òṣèré, olóòtú àti olùdarí sinimá-àgbéléwò ọmọ bíbí Yorùbá, ní Ìgbómìnà láti ìpínlẹ̀ Kwara lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Bàbá rẹ̀ ni gbajúgbajà òṣèré sinimá àgbéléwò nígbà kan rí, ṣùgbọ́n tí ó ti di olóògbé, Adeyemi Afolayan, tí gbogbo ènìyàn mọ̀ sí Ade Love[1] [2]

Ìgbà èwe àti aáyan ìkẹ́kọ̀ọ́ rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Kúnlé jẹ́ ọmọ bíbí Ìgbómìnà pọ́ńbélé láti ìpínlẹ̀ Kwara gẹ́gẹ́ bí a ti sọ ṣáájú. Gbajúgbajà òṣèré sinimá àgbéléwò àná ni bàbá rẹ̀ Ade Love. Kúnlé kàwé gboyè nínú ìmọ̀ ìsúná ọ̀rọ̀-ajé. Ó ṣiṣẹ́ nílé ìfowópamọ́ fún ìgbà díẹ̀ kí ó tó dára pọ̀ mọ́ ìṣe sinimá àgbéléwò ṣíṣe lọ́dún 2015. Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ó ti ń kópa ní ìwọ̀nba kí ó tó di àkókò yìí. Kúnlé máa ń kópa nínú sinimá àgbéléwò lédè Yorùbá àti Gẹ̀ẹ́sì. Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ni sinimá-àgbéléwò tí ó ti kópa tó ṣòódó. Ọ̀pọ̀lọpọ̀ sìn ni àmìn ẹ̀yẹ tí ó gbà gẹ́gẹ́ bí eléré tíátà.[3] [4]


Awọn àmì ẹ̀yẹ[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Year Award Category Film Result Ref
2019 Best of Nollywood Awards Director of the Year Diamond in the Sky Wọ́n pèé [5]
2021 Net Honours Most Searched Actor Wọ́n pèé [6]
2023 Africa Magic Viewers' Choice Awards Best Indigenous Language – Yoruba Anikulapo Gbàá [7]
Best Movie West Africa Yàán
Best Overall Movie Gbàá
Best Director Yàán

Àwọn Ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "Kunle Afolayan Biography, History, Asset and Net Worth - Austine Media". Austine Media. 2018-05-20. Retrieved 2019-12-09. 
  2. "Kunle Afolayan". Leadership Newspaper. 2019-04-07. Retrieved 2019-12-09. 
  3. Hoad, Phil (2012-10-30). "Out of Africa: Kunle Afolayan bids to bring Nollywood cinema to the world". the Guardian. Retrieved 2019-12-09. 
  4. "BIOGRAPHY". OKIKI AFOLAYAN CONCEPTS. 2018-01-31. Archived from the original on 2019-12-09. Retrieved 2019-12-09. 
  5. Bada, Gbenga (2019-12-15). "BON Awards 2019: 'Gold Statue', Gabriel Afolayan win big at 11th edition". Pulse Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2021-10-10.  Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  6. "Net Honours - The Class of 2021". Nigerian Entertainment Today (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2021-09-07. 
  7. "Full List: Here are all our AMVCA 9 Nominees". AMVCA - Full List: Here are all our AMVCA 9 Nominees (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2023-04-23. [Ìjápọ̀ tí kò ṣiṣẹ́ mọ́]