Kunle Afolayan
Kunle Afolayan | |
---|---|
Kunle Afolayan at the 2014 Africa Magic Viewers Choice Awards | |
Ọjọ́ìbí | 30 Oṣù Kẹ̀sán 1974 Ebute Metta, Lagos State, Nàìjíríà |
Ibùgbé | Magodo, Ikeja, Lagos State, Nàìjíríà |
Orílẹ̀-èdè | Nàìjíríà |
Iṣẹ́ | |
Olólùfẹ́ | Tolu Afolayan |
Àwọn ọmọ | 4 |
Parent(s) | Ade Love - father |
Àwọn olùbátan |
|
Kunle Afolayan (tí wọ́n bí ní ọjọ́ ọgbọ̀n oṣù kẹsàn-án ọdún 1974) jẹ́ gbajúmọ̀ òṣèré, olóòtú àti olùdarí sinimá-àgbéléwò ọmọ bíbí Yorùbá, ní Ìgbómìnà láti ìpínlẹ̀ Kwara lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Bàbá rẹ̀ ni gbajúgbajà òṣèré sinimá àgbéléwò nígbà kan rí, ṣùgbọ́n tí ó ti di olóògbé, Adeyemi Afolayan, tí gbogbo ènìyàn mọ̀ sí Ade Love[1] [2]
Ìgbà èwe àti aáyan ìkẹ́kọ̀ọ́ rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
Kúnlé jẹ́ ọmọ bíbí Ìgbómìnà pọ́ńbélé láti ìpínlẹ̀ Kwara gẹ́gẹ́ bí a ti sọ ṣáájú. Gbajúgbajà òṣèré sinimá àgbéléwò àná ni bàbá rẹ̀ Ade Love. Kúnlé kàwé gboyè nínú ìmọ̀ ìsúná ọ̀rọ̀-ajé. Ó ṣiṣẹ́ nílé ìfowópamọ́ fún ìgbà díẹ̀ kí ó tó dára pọ̀ mọ́ ìṣe sinimá àgbéléwò ṣíṣe lọ́dún 2015. Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ó ti ń kópa ní ìwọ̀nba kí ó tó di àkókò yìí. Kúnlé máa ń kópa nínú sinimá àgbéléwò lédè Yorùbá àti Gẹ̀ẹ́sì. Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ni sinimá-àgbéléwò tí ó ti kópa tó ṣòódó. Ọ̀pọ̀lọpọ̀ sìn ni àmìn ẹ̀yẹ tí ó gbà gẹ́gẹ́ bí eléré tíátà.[3] [4]
Awọn àmì ẹ̀yẹ[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
Year | Award | Category | Film | Result | Ref |
---|---|---|---|---|---|
2019 | Best of Nollywood Awards | Director of the Year | Diamond in the Sky | Wọ́n pèé | [5] |
2021 | Net Honours | Most Searched Actor | Wọ́n pèé | [6] | |
2023 | Africa Magic Viewers' Choice Awards | Best Indigenous Language – Yoruba | Anikulapo | Gbàá | [7] |
Best Movie West Africa | Yàán | ||||
Best Overall Movie | Gbàá | ||||
Best Director | Yàán |
Àwọn Ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
- ↑ "Kunle Afolayan Biography, History, Asset and Net Worth - Austine Media". Austine Media. 2018-05-20. Retrieved 2019-12-09.
- ↑ "Kunle Afolayan". Leadership Newspaper. 2019-04-07. Retrieved 2019-12-09.
- ↑ Hoad, Phil (2012-10-30). "Out of Africa: Kunle Afolayan bids to bring Nollywood cinema to the world". the Guardian. Retrieved 2019-12-09.
- ↑ "BIOGRAPHY". OKIKI AFOLAYAN CONCEPTS. 2018-01-31. Archived from the original on 2019-12-09. Retrieved 2019-12-09.
- ↑ Bada, Gbenga (2019-12-15). "BON Awards 2019: 'Gold Statue', Gabriel Afolayan win big at 11th edition". Pulse Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2021-10-10. Unknown parameter
|url-status=
ignored (help) - ↑ "Net Honours - The Class of 2021". Nigerian Entertainment Today (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2021-09-07.
- ↑ "Full List: Here are all our AMVCA 9 Nominees". AMVCA - Full List: Here are all our AMVCA 9 Nominees (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2023-04-23.[Ìjápọ̀ tí kò ṣiṣẹ́ mọ́]