Dorcas Ajoke Adesokan
Ìrísí
Dorcas Ajoke Adesokan (tí a bí ní ọjọ́ karùn-ún, oṣụ́ keje, ọdún 1998) jẹ́ ọmọ orílẹ-èdè Naijiria tó ń gbá bọ́ọ̀lù badminton.[1]
Iṣẹ́ rẹ́
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Ní ọdún 2014, ó jẹ ẹ̀bùn fún ipò kẹta ní ìdíje ti ilẹ̀ Africa.[2] Ní oṣù kẹfà, ó jẹ́ olúborí nínú ìdíje ti Lagos International Tournaments.[3]
Ní ọdún 2019, ó kópa nínú ìdíje ti ilẹ̀ Africa, ó sì gba ẹ̀bùn kan fún ipò kìíní àti ẹ̀bùn méjì fún ipò kejì.[4]
Ní ọdún 2021, ó kópa nínú ìdíje ti 2020 Summer Olympics.[5][6]
Àṣeyọrí rẹ̀
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Eré ti ilẹ̀ African
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Obìnrin nìkan
| Year | Venue | Opponent | Score | Result |
|---|---|---|---|---|
| 2019 | Ain Chock Indoor Sports Center, Casablanca, Morocco | 19–21, 18–21 |
Àdàlú ẹ̀
| Year | Venue | Partner | Opponent | Score | Result |
|---|---|---|---|---|---|
| 2019 | Ain Chock Indoor Sports Center,
Casablanca, Morocco |
9–21, 16–21 |
African Championships
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Obìnrin nìkan
| Year | Venue | Opponent | Score | Result |
|---|---|---|---|---|
| 2014 | Lobatse Stadium, Gaborone, Botswana | 4–21, 15–21 | ||
| 2017 | John Barrable Hall, Benoni, South Africa | 21–13, 19–21, 13–21 | ||
| 2018 | Salle OMS Harcha Hacéne, Algiers, Algeria | 16–21, 19–21 | ||
| 2019 | Alfred Diete-Spiff Centre, Port Harcourt, Nigeria | 21–12, 21–13 | ||
| 2020 | Cairo Stadium Hall 2, Cairo, Egypt | 19–21, 16–21 |
Àdàlú ẹ̀
| Year | Venue | Partner | Opponent | Score | Result |
|---|---|---|---|---|---|
| 2017 | John Barrable Hall,
Benoni, South Africa |
4–21, 26–24, 18–21 | |||
| 2019 | Alfred Diete-Spiff Centre,
Port Harcourt, Nigeria |
21–14, 20–22, 21–17 | |||
| 2020 | Cairo Stadium Hall 2, | 14–21, 17–21 |
Àdàlú ẹ̀
| Year | Venue | Partner | Opponent | Score | Result |
|---|---|---|---|---|---|
| 2014 | Lobatse Stadium,
Gaborone, Botswana |
17–21, 16–21 |
African Youth Games
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Obìnrin nìkan
| Year | Venue | Opponent | Score | Result |
|---|---|---|---|---|
| 2014 | Otse Police College, Gaborone, Botswana | 21–12, 21–15 |
Àdàlú ẹ̀
| Year | Venue | Partner | Opponent | Score | Result |
|---|---|---|---|---|---|
| 2014 | Otse Police College,
Gaborone, Botswana |
21–15, 21–15 |
BWF International Challenge/Series (12 titles, 5 runners-up)
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Obìnrin nìkan
| Year | Tournament | Opponent | Score | Result |
|---|---|---|---|---|
| 2017 | Benin International | 21–7, 21–18 | Winner | |
| 2018 | Côte d'Ivoire International | 21–10, 21–12 | Winner | |
| 2018 | Zambia International | 21–18, 21–15 | Winner | |
| 2018 | South Africa International | 22–20, 21–12 | Winner | |
| 2019 | Cameroon International | 19–21, 12–21 | Runner-up | |
| 2019 | Zambia International | 20–22, 21–18, 21–18 | Winner |
Àdàlú ẹ̀
| Year | Tournament | Partner | Opponent | Score | Result |
|---|---|---|---|---|---|
| 2013 | Kenya International | Bridget Shamim Bangi
Margaret Nankabirwa |
21–18, 21–9 | Winner | |
| 2013 | Mauritius International | 15–21, 16–21 | Runner-up | ||
| 2014 | Uganda International | 21–14, 9–21, 12–21 | Runner-up | ||
| 2014 | Lagos International | 21–19, 22–20 | Winner | ||
| 2017 | Benin International | 21–18, 16–21, 21–12 | Winner | ||
| 2019 | Ghana International | 11–21, 11–21 | Runner-up |
Àdàlú ẹ̀
| Year | Tournament | Partner | Opponent | Score | Result |
|---|---|---|---|---|---|
| 2013 | Nigeria International | 21–12, 21–17 | Winner | ||
| 2014 | Uganda International | 15–21, 21–10, 21–18 | Winner | ||
| 2014 | Nigeria International | 11–8, 4–11, 11–7, 10–11, 8–11 | Runner-up | ||
| 2018 | Côte d'Ivoire International | 21–9, 21–15 | Winner | ||
| 2018 | Zambia International | 21–19, 23–21 | Winner |
Àwọn ìtọ́kasí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ "Players: Dorcas Ajoke Adesokan". Badminton World Federation. Retrieved 14 October 2016.
- ↑ "Paul and Adesokan; Africa's Best Juniors". Badminton Confederation of Africa. Retrieved 14 October 2016.
- ↑ "Host Win Women's and Mixed Doubles". Badminton Confederation of Africa. Retrieved 14 October 2016.
- ↑ Àṣìṣe ìtọ́kasí: Invalid
<ref>tag; no text was provided for refs namedra - ↑ "Tokyo 2020 Olympics: Nigeria aiming to break from the past". Vanguard. 24 July 2021. Retrieved 8 September 2021.
- ↑ "Adesokan Dorcas Ajoke". Tokyo Organising Committee of the Olympic and Paralympic Games. Archived from the original on 8 September 2021. Retrieved 8 September 2021.