Rauf Aregbesola
Jump to navigation
Jump to search
Rauf Aregbesola | |
---|---|
Gomina Ipinle Osun | |
Lọ́wọ́lọ́wọ́ | |
Ó gun orí àga 27 November 2010 | |
Asíwájú | Olagunsoye Oyinlola |
Àwọn àlàyé onítòhún | |
Ọjọ́ìbí | 25 Oṣù Kàrún 1957 |
Ọmọorílẹ̀-èdè | Nigerian |
Ẹgbẹ́ olóṣèlú | Action Congress of Nigeria |
Rauf Aregbesola A bii ni ojo keedogbon osu karun-un odun 1957. O je agba oloselu omo ile Yoruba lati ipinle Osun lorile-ede Naijiria. Won dibo yan-an gegebi Gomina Ipinle Osun ni odun 2010 titi o fi fipo naa Sile ni odun 2018 leyin to o lo saa ikeji re tan. Gboyega Oyetola ni Rauf Aregbesola fa agbara Gomina ipinle Osun le lowo leyin saa re[1]. Ni odun 2019, Aare Muhammadu Buhari yan-an gegebi Minisita alanbojuto eto abele (Minister for Interior) lorile-ede Naijiria[2]
![]() |
Àyọkà yìí tàbí apá rẹ̀ únfẹ́ àtúnṣe sí. Ẹ le fẹ̀ jù báyìí lọ tàbí kí ẹ ṣàtúnṣe rẹ̀ lọ́nà tí yíò mu kúnrẹ́rẹ́. Ẹ ran Wikipedia lọ́wọ́ láti fẹ̀ẹ́ jù báyìí lọ. |
Itokasi[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
- ↑ "My successor, Oyetola, doesn't have my 'swagger' - Aregbesola - Premium Times Nigeria". Premium Times Nigeria. 2018-11-17. Retrieved 2019-09-20.
- ↑ Bankole; Bankole (2019-08-21). "Profile of Interior Minister, Ogbeni Rauf Aregbesola". Vanguard News. Retrieved 2019-09-20.