Sa'idu Ahmed Alkali
Ìrísí
Sa'idu Ahmed Alkali | |
|---|---|
| Senator of the Federal Republic of Nigeria from Gombe State North District | |
| Asíwájú | Usman Bayero Nafada |
| Àwọn àlàyé onítòhún | |
| Ọjọ́ìbí | 12 Oṣù Kejì 1969 Gombe State, Nigeria |
| Ọmọorílẹ̀-èdè | Nigerian |
| Ẹgbẹ́ olóṣèlú | All ProgressiveCongress APC |
| Àwọn òbí | Khadi Ahmed Saidu Alkali |
Sa'idu Ahmed Alkali jẹ́ olósèlú ní ilẹ̀ Nàìjíríà. A bí Alkali ní ọjọ́ kejìlá oṣù Èrèlé ọdún 1969 ní agbègbè Dukku ní apá ilà-oòrùn àríwá órílè-èdè Nàìjíríà.[1] Ní ọjọ́ kẹrìndínlógún oṣù Ògún ọdún 2023, ó jẹ adaríi ìjọba l’óri ọ̀rọ̀ ètò ìrìnà ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. [2]
Ẹ̀kọ́ àti Iṣẹ́
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Ó ka Ètò ọ̀rọ̀ ajé (Economics) ní ilé-ẹ̀kọ́ gíga ti Maiduguri ní ìpínlẹ̀ Borno. Ó ṣiṣẹ́ pẹ̀lú ìgbìmọ̀ ìjọba-abẹ́lé ti Dukku, kí ó tó wá ṣiṣẹ́ ní àjọ tó ń bójútó ọ̀rọ̀ ìdìbò ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà (INEC).[1]
| Àyọkà yìí tàbí apá rẹ̀ únfẹ́ àtúnṣe sí. Ẹ le fẹ̀ jù báyìí lọ tàbí kí ẹ ṣàtúnṣe rẹ̀ lọ́nà tí yíò mu kúnrẹ́rẹ́. Ẹ ran Wikipedia lọ́wọ́ láti fẹ̀ẹ́ jù báyìí lọ. |
Àwọn Ìtọ́kasí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- 1 2 Yaya, Haruna Gimba (2023-08-02). "Things to know about Sa'idu Alkali, three-term Senator...". Daily Trust. Retrieved 2025-10-02.
- ↑ Release, Press (2025-05-23). "The Quiet Thunder of Progress Under Saidu Alkali, By Aisha U Ahmed". Premium Times Nigeria. Retrieved 2025-10-02.