Ayo Adeseun

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
(Àtúnjúwe láti Ayoade Ademola Adeseun)
Ayoade Ademola Adeseun
Aṣojú àárín Ọ̀yọ́ ní ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà
Lọ́wọ́lọ́wọ́
Ó gun orí àga
Oṣù karún, Ọdún 2011
AsíwájúTeslim Folarin
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbí1 Oṣù Kínní 1953 (1953-01-01) (ọmọ ọdún 71)
Ẹgbẹ́ olóṣèlúAction Congress of Nigeria (ACN)

Ayoade Ademola Adeseun (bíi ní Ọjọ́ kínín Oṣù kínín Ọdún 1953) jẹ́ olóṣèlú ọmọ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà tí wọ́n dìbò yàn wọlé gẹ́gẹ́ bí aṣojú ààrín Ọyọ́, ìpínlẹ̀ Ọyọ ní ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà ti ilẹ̀ Nàìjíríà. Ó jẹ́ aṣojú ní ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin láti ọdún 2011 sí 2015 lábẹ́ ẹgbẹ́ òṣèlú Action Congress of Nigeria (ACN).[1][2][3]

Àwọn ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "Collated Senate results". INEC. Archived from the original on 2011-04-19. Retrieved 2011-04-27. 
  2. "OYO HON. AYOADE ADEMOLA ADESEUN PDP". Office of the Speaker of the House. Archived from the original on 2011-10-08. Retrieved 2011-04-27. 
  3. Ademola BABALOLA (23 March 2011). "Alao-Akala’s govt, not Folarin, killed Eleweomo, says gov’s kinsman". Nigerian Compass. Retrieved 2011-04-27.