Oluremi Tinubu
Oluremi Tinubu ( tí a bí ní ọjọ́ kọkàndínlógún, oṣù kẹsàn-án ọdún 1960) jẹ́ olóṣèlú ọmọ , bíbí Ìpínlẹ̀ Ògùn lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà.[1] Ó jẹ́ Ìyàwó Bọ́lá Ahmed Tinúbú, ẹni tí ó jẹ́ Gómìnà Ìpínlẹ̀ Èkó ní ọdún 1999 sí ọdún 2007. Rẹ̀mí tún jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ ilé-aṣòfin-Àgbà lowolowo (Senator) tí ó ń ṣojú fún Ẹkùn Àárín gbùngbùn Ìpínlẹ̀ Èkó,fún ìgbà Ìkẹ́ta ní Ilé Alàgbà Nàìjíríà.[2]
Ibèrè ayé àti èkó[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
Olúrèmí Tinúbú jé àbíkéhìn nínú omo méjìlá; ó sì dàgbà ní ìpínlè Ogun State.
Olúrèmí ka èkó ilé-ìwé gíga ní University Ifè, àti Adeyemi College of Education.
Isé Olósèlú[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
Olúrèmí Tinúbú je arabinrin àkókó tì'lu èkó nígbà ti oko re, Bólá Tinúbú, je gomina. Beeni o so da New Era Foundation, eyi to was fun idagbasoke ati igbega awon odo, ati lati kpolongo imototo awujo.
![]() |
Àyọkà yìí tàbí apá rẹ̀ únfẹ́ àtúnṣe sí. Ẹ le fẹ̀ jù báyìí lọ tàbí kí ẹ ṣàtúnṣe rẹ̀ lọ́nà tí yíò mu kúnrẹ́rẹ́. Ẹ ran Wikipedia lọ́wọ́ láti fẹ̀ẹ́ jù báyìí lọ. |
Àwọn Ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
- ↑ Themes, AccessPress (2019-08-12). "About Oluremi – Oluremi Tinubu @ Senate". Oluremi Tinubu @ Senate. Retrieved 2019-09-25.
- ↑ "Oluremi Tinubu". Wikipedia. 2012-05-20. Retrieved 2019-09-25.