Victor Ndoma-Egba

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
(Àtúnjúwe láti Victor Ndoma Egbe)
Victor Ndoma-Egba
Aṣojú ní ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà ti ilẹ̀ Nàìjíríà
Lọ́wọ́lọ́wọ́
Ó gun orí àga
Odún 2003
ConstituencyÀárín Cross River
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbí8 Oṣù Kẹta 1956 (1956-03-08) (ọmọ ọdún 68)
Ẹgbẹ́ olóṣèlúPeople's Democratic Party (PDP)
ProfessionAmòfin àti olóṣèlú

Victor Ndoma-Egba (bíi ní ọjọ́ kẹjọ oṣù kẹta ọdún 1956) jẹ́ olóṣèlú ọmọ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà tí wọ́n dìbò yàn wọlé gẹ́gẹ́ bí aṣojú ní ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà ti ilẹ̀ Nàìjíríà láti ọdún 2003.[1]

Ìpinlẹ̀ṣẹ̀ ayé rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Wọ́n bí Victor Ndoma-Egba ní ọjọ́ kẹjọ oṣù kẹta ọdún 1956 ní ilù Ikom, Ìpínlẹ̀ Cross River. Ó gba ìwé ẹ̀rí àkọ́kọ́ nínú ìmọ̀ òfin láti University of Lagos. Wọ́n pèé sí àwùjọ amòfin gẹ́gẹ́ bí agbẹjọ́rò ní ọdún 1978 tí ó si di Senior Advocate of Nigeria (SAN) ní ọdún 2004.[2] Ó ti fi ìgbàkan jẹ́ alága Nigerian Bar Association ti ẹ̀ka Calabar.

Àwọn ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "Sen. Victor Ndoma-Egba". National Assembly of Nigeria. Archived from the original on 2008-06-07. Retrieved 2009-09-16. 
  2. "Senator Victor Ndoma-Egba: A Leader For The Ages". Times of Nigeria. July 10, 2009. Retrieved 2009-09-16.